a
Hb 12.5
,
6
.
Proverbs 3:11-12
11
a
Ọmọ mi, má ṣe kẹ́gàn ìbáwí
Olúwa
má sì ṣe bínú nígbà tí ó bá ń bá ọ wí,
12
Nítorí
Olúwa
a máa bá àwọn tí ó fẹ́ràn wí
bí baba ti í bá ọmọ tí ó bá nínú dídùn sí wí.
Copyright information for
YorBMYO